Gbogbo Islam Library

114 - Mankind - An-Nās

:1

Sọ pé: “Mo sá di Olúwa àwọn ènìyàn,

:2

Ọba àwọn ènìyàn,

:3

Ọlọ́hun àwọn ènìyàn,1

:4

níbi aburú (Èṣù) oníròyíròyí, olùsásẹ́yìn (fún ẹni tó bá ń dárúkọ Allāhu.

:5

(Èṣù ni) ẹni tí ó ń kó ròyíròyí sínú àwọn ọkàn ènìyàn.

:6

(Èṣù náà) wà nínú àwọn àlùjànnú àti àwọn ènìyàn.”